Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

July 15, 2011

Ẹ̀dà Tó Wà Fún Ìkẹ́kọ̀ọ́

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:

August 29, 2011–September 4, 2011

Jèhófà Ń Fìfẹ́ Tọ́ Wa Sọ́nà, Ṣé Wàá Tẹ̀ Lé Ìtọ́sọ́nà Rẹ̀?

OJÚ ÌWÉ 10

ÀWỌN ORIN TÍ A Ó KỌ: 26, 3

September 5-11, 2011

Ṣé Wàá Gbọ́ Ìkìlọ̀ Tó Ṣe Kedere Tí Jèhófà Ń Fún Wa?

OJÚ ÌWÉ 15

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 65, 52

September 12-18, 2011

Kí Ni Ìsinmi Ọlọ́run?

OJÚ ÌWÉ 24

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 19, 27

September 19-25, 2011

Ṣé O Ti Wọnú Ìsinmi Ọlọ́run?

OJÚ ÌWÉ 28

ÀWỌN ORIN TÁ A Ó KỌ: 134, 24

Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá A Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé

ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ 1, 2 OJÚ ÌWÉ 10 sí 19

Nítorí pé Jèhófà nífẹ̀ẹ́ wa, ó máa ń kìlọ̀ fún wa nípa àwọn ewu tó lè mú ká yà kúrò lójú ọ̀nà tó lọ sí ìyè àìnípẹ̀kun. Nínú àwọn àpilẹ̀kọ méjì yìí, a jíròrò ewu mẹ́fà tá a gbọ́dọ̀ ṣọ́ra fún àti bó ṣe yẹ ká ṣọ́ra fún wọn.

ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ 3, 4 OJÚ ÌWÉ 24 sí 32

Bíbélì sọ pé lẹ́yìn tí Jèhófà dá èèyàn, Ó “sinmi” ní ọjọ́ keje. (Héb. 4:4) Àpilẹ̀kọ kẹta tó wà fún ìkẹ́kọ̀ọ́ máa ṣàlàyé ìdí tí Ọlọ́run fi sinmi ní ọjọ́ keje àti ọ̀nà tí ìsinmi rẹ̀ gbà kàn wá. Nínú àpilẹ̀kọ kẹrin tó wà fún ìkẹ́kọ̀ọ́, a máa rí díẹ̀ lára ọ̀nà tá a lè gbà fi hàn pé a ti wọnú ìsinmi Jèhófà.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ

3 Ilé Ìṣọ́ Tá A Fi Èdè Gẹ̀ẹ́sì Tó Rọrùn Kọ

4 Ilé Ẹjọ́ Dá Àwọn Èèyàn Jèhófà Láre!

20 Mo Bẹ̀rù Ikú, Àmọ́ Ìyè “Lọ́pọ̀ Yanturu” Ni Mò Ń Retí Báyìí