Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2011

Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2011

Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2011

Ó ń tọ́ka sí Ilé Ìṣọ́ tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

A Jẹ́ “Olùgbé fún Ìgbà Díẹ̀” Nínú Ayé Búburú, 11/15

Bá A Ṣe Lè Fi Ọwọ́ Pàtàkì Mú Iṣẹ́ Ìsìn Wa sí Jèhófà, 4/15

Bọ̀wọ̀ fún Ìgbéyàwó Tó Jẹ́ Ẹ̀bùn Ọlọ́run, 1/15

“Èso Ti Ẹ̀mí” Ń Fi Ògo fún Ọlọ́run, 4/15

Ẹ Fi Ìfaradà Sá Eré Ìje Náà, 9/15

Ẹ Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà bí Òpin Ti Ń Sún Mọ́lé, 3/15

Ẹ Kọ́ Àwọn Míì Kí Wọ́n Lè Tóótun fún Àǹfààní Iṣẹ́ Ìsìn, 11/15

Ẹ Máa Lépa Àlàáfíà, 8/15

Ẹ Máa Rìn ní Ìbámu Pẹ̀lú Ẹ̀mí Kẹ́ Ẹ Lè Jogún Ìyè àti Àlàáfíà, 11/15

Ẹ Máa Ṣe Àwọn Ìpinnu Tó Máa Gbé Orúkọ Ọlọ́run Ga, 4/15

“Ẹ Máa Ṣe Olùṣọ́ Àgùntàn Agbo Ọlọ́run Tí Ń Bẹ Lábẹ́ Àbójútó Yín,” 6/15

Ẹ̀mí Mímọ́ Ń Fún Wa Lágbára Ká Lè Borí Àdánwò Èyíkéyìí, 1/15

Ẹ̀mí Mímọ́ Ń Fún Wa Lágbára Ká Lè Kojú Ìdẹwò Ká sì Borí Ìrẹ̀wẹ̀sì, 1/15

Ẹ̀mí Mímọ́ Ni Ọlọ́run Lò Nígbà Ìṣẹ̀dá, 2/15

Ẹ̀mí Ọlọ́run Darí Àwọn Kristẹni ní Ọ̀rúndún Kìíní Ó sì Ń Darí Àwa Náà Lónìí, 12/15

Ẹ̀mí Ọlọ́run Darí Àwọn Olóòótọ́ Ayé Ìgbàanì, 12/15

Ẹ̀mí Ọlọ́run Ni Kó O Gbà, Má Ṣe Gba Ẹ̀mí Ayé, 3/15

“Ẹ Ní Ẹ̀mí Ìkanisí fún Àwọn Tí Ń Ṣiṣẹ́ Kára Láàárín Yín,” 6/15

Ẹ Ran Àwọn Ọkùnrin Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè Tẹ̀ Síwájú Nípa Tẹ̀mí, 11/15

Ẹ Sáré . . . Kí Ọwọ́ Yín Lè Tẹ̀ Ẹ́,” 9/15

Ẹ Wà Lójúfò Bíi Ti Jeremáyà, 3/15

Ẹ Wà ní Ìmúratán! 3/15

Ẹ̀yin Ìdílé Kristẹni—“Ẹ Wà Lójúfò,” 5/15

Ẹ̀yin Ìdílé Kristẹni—“Ẹ Wà Ní Ìmúratán,” 5/15

Fi Gbogbo Ọkàn Rẹ Nífẹ̀ẹ́ Òdodo, 2/15

Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà, “Ọlọ́run Ìtùnú Gbogbo,” 10/15

Ìgbọ́kànlé Kíkún Nínú Jèhófà Ń Mú Ká Ní Ìgboyà, 5/15

Ìhìn Rere Tó Yẹ Kí Gbogbo Èèyàn Gbọ́, 6/15

‘Ìjìnlẹ̀ Ọgbọ́n Ọlọ́run Mà Pọ̀ O!’ (Ro 11), 5/15

Ìmọ̀ràn Ọlọgbọ́n Fáwọn Tí Kò Ṣègbéyàwó Àtàwọn Tó Ṣègbéyàwó, 10/15

Jèhófà Ń Fìfẹ́ Tọ́ Wa Sọ́nà, Ṣé Wàá Tẹ̀ Lé Ìtọ́sọ́nà Rẹ̀? 7/15

Jèhófà Ni Ìpín Mi, 9/15

Jèhófà, “Ọlọ́run Tí Ń Fúnni Ní Àlàáfíà,” 8/15

Kí Ni Ìsinmi Ọlọ́run? 7/15

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Jẹ́ Kí Ẹ̀mí Ọlọ́run Máa Darí Wa? 12/15

Lo Ẹ̀bùn Wíwà Láìní Ọkọ Tàbí Aya Lọ́nà Tó Dára Jù Lọ, 1/15

‘Má Ṣe Gbára Lé Òye Tìrẹ,’ 11/15

Ǹjẹ́ O Kórìíra Ìwà Àìlófin? 2/15

Ǹjẹ́ Ò Ń Fi Jèhófà Ṣe Ìpín Rẹ? 9/15

Ọlọ́run Dámọ̀ràn Ìfẹ́ Rẹ̀ fún Wa, 6/15

Rírí Ìtẹ́wọ́gbà Ọlọ́run Ló Máa Mú Ká Jogún Ìyè Àìnípẹ̀kun, 2/15

“Sá Di Orúkọ Jèhófà,” 1/15

Ṣé Àpẹẹrẹ Rere Ló Jẹ́ fún Ẹ àbí Ìkìlọ̀? 12/15

Ṣé Eré Ìtura Tó O Yàn Máa Ṣe Ẹ́ Láǹfààní? 10/15

Ṣé Jèhófà Mọ̀ Ẹ́? 9/15

Ṣé Ò Ń Jẹ́ Kí Ẹ̀mí Ọlọ́run Máa Darí Rẹ? 4/15

Ṣé O Ti Wọnú Ìsinmi Ọlọ́run? 7/15

Ṣé Wàá Gbọ́ Ìkìlọ̀ Tó Ṣe Kedere Tí Jèhófà Ń Fún Wa? 7/15

Ta Ló Ṣe Pàtàkì Jù Lọ ní Ìgbésí Ayé Rẹ? 5/15

“Tu Gbogbo Àwọn Tí Ń Ṣọ̀fọ̀ Nínú,” 10/15

Wọ́n Retí Mèsáyà, 8/15

Wọ́n Rí Mèsáyà! 8/15

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

“Àǹfààní Ìfúnni Onínúrere” (ọrẹ), 11/15

Àwọn Àpéjọ Àgbègbè “Kí Ìjọba Ọlọ́run Dé!” 6/1

Àwọn Àpéjọ Àgbègbè Nílẹ̀ Rọ́ṣíà, 3/1

Àwọn Ìsọfúnni Tó Máa Ń Wà Nínú Ìròyìn Iṣẹ́ Ìsìn Wa Ọdọọdún, 8/15

Ayẹyẹ Ìkẹ́kọ̀ọ́yege Ilé Ẹ̀kọ́ Gílíádì, 2/1, 8/1

Gbèjà Orúkọ Rere (Rọ́ṣíà), 5/1

Ìdí fún Ayọ̀ Yíyọ̀ (ètò), 3/15

Ilé Ẹjọ́ Dá Àwọn Èèyàn Jèhófà Láre! (Rọ́ṣíà), 7/15

Ilé Ìṣọ́ Tá A Fi Èdè Gẹ̀ẹ́sì Tó Rọrùn Kọ (ìwé ìròyìn), 7/15

Ìpàdé Ọdọọdún, 8/15

Lẹ́tà Láti . . . , 3/1, 6/1, 9/1, 12/1

Ṣé Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Máa Ń Gba Ìtọ́jú Lọ́dọ̀ Àwọn Dókítà? 2/1

“Wọ́n Kọ̀ Jálẹ̀, Ó Yẹ Ká Bọ̀wọ̀ fún Wọn” (Ìjọba Násì, Orílẹ̀-èdè Jámánì), 10/1

BÍBÉLÌ

Abala Àwọn Ọ̀dọ́, 1/1, 3/1, 5/1, 7/1, 9/1, 11/1

Àwọn Wo Lára Àwọn Tó Kọ Ìwé Mímọ́ Kristẹni Lédè Gíríìkì Ló Wà ní Pẹ́ńtíkọ́sì Ọdún 33 Sànmánì Kristẹni? 12/1

Ìgbà Tí Wọ́n Kọ Ọ́, 6/1

Ìsapá Zamora Láti Túmọ̀ Ìwé Mímọ́ Lọ́nà Tó Péye, 12/1

Máa Ń Yí Ìgbésí Ayé Àwọn Èèyàn Pa Dà, 2/1, 4/1, 5/1, 7/1, 8/1, 10/1, 11/1

Mẹ́fà Nínú Àsọtẹ́lẹ̀ Bíbélì Tó Ń Ṣẹ Lójú Wa, 5/1

Olivétan—‘Onírẹ̀lẹ̀ Tó Túmọ̀’ Bíbélì, 9/1

Ṣé Kíkẹ́kọ̀ọ́ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Máa Ń Gbádùn Mọ́ Ẹ? 5/15

Wákàtí Ọjọ́, 5/1

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

Bí O Ṣe Lè Yan Ọ̀rẹ́ Rere? 12/1

Bíi Ti Fíníhásì Bó O Bá Dojú Kọ Àwọn Ipò Tó Nira, 9/15

Ẹ Jẹ́ Ká Jọ Máa Yọ̀! 10/15

Ẹ Má Ṣe Fi Èrò Èké Tan Ara Yín Jẹ, 3/15

Fòye Mọ Ẹ̀rí Tó Fi Hàn Pé Ọlọ́run Ń Tọ́ Wa Sọ́nà, 4/15

Ìbéèrè Tó Dá Lórí Bíbélì, Kí Ló Yẹ Kí N Ṣe Tí Mo Bá Nílò Ìmọ̀ràn Nípa Ìṣòro Kan? 10/15

“Ìgbà Nínífẹ̀ẹ́ àti Ìgbà Kíkórìíra,” 12/1

‘Ìgbọràn Sàn Ju Ẹbọ Lọ,’ 2/15

Ìjọsìn Ìdílé, 8/15

Íńtánẹ́ẹ̀tì, 8/15

Ipa Tí Ọmọ Lè Ní Lórí Àjọṣe Ọkọ àti Aya, 5/1

Ìsapá Náà Tó Bẹ́ẹ̀ Ó Jù Bẹ́ẹ̀ Lọ! (Ìjọsìn Ìdílé), 2/15

Kí Làwọn Bàbá Lè Ṣe Tí Àjọṣe Wọn Pẹ̀lú Ọmọkùnrin Wọn Kò Fi Ní Bà Jẹ́? 11/1

Kí Ló Lè Mú Kí Ìdílé Rẹ Jẹ́ Aláyọ̀? 10/1

Kí Ló Lè Mú Kí Ìgbéyàwó Wà Pẹ́ Títí? 2/1

Kọ́ Àwọn Ọmọ Láti Máa Bọ̀wọ̀ Fúnni, 2/15

Kọ́ Àwọn Ọmọ ní Ohun Tó Tọ́ Nípa Ìbálòpọ̀, 2/1

Kọ́ Ọmọ Rẹ, 2/1, 4/1, 6/1, 8/1, 10/1, 12/1

Má Ṣe Jẹ́ Kí Àìlera Ba Ayọ̀ Rẹ Jẹ́, 12/15

Má Ṣe Kọ Àwọn Tẹ́ Ẹ Jọ Jẹ́ Onígbàgbọ́ Sílẹ̀ Láé, 3/15

“Máa Bá A Nìṣó ní Ṣíṣọ́nà” 10/15

Máa Bọ̀wọ̀ fún Ọkọ Tàbí Aya Rẹ, 8/1

Máa Ṣe Àṣàrò Lórí Ohun tí Jèhófà Ti Ṣe fún Ẹ, 1/15

Mọyì Àwọn Ìbùkún Tó O Ní? 2/15

“Mú Kí Ọ̀nà Rẹ Yọrí sí Rere,” 6/15

Olóòótọ́ Nínú Ayé Aláìṣòótọ́, 4/15

Owó Orí, 9/1

Ṣé Ó Yẹ Kí Òbí Kọ́ Àwọn Ọmọ Nípa Ìbálòpọ̀? 11/1

Ṣó Yẹ Kí Àwọn Ọmọdé Ṣe Ìrìbọmi? 6/15

Tọkọtaya, Ẹ Kọ́ Bí Ẹ Ṣe Máa Jẹ́ Ẹni Tẹ̀mí, 11/1

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

“Alábòójútó Rere àti Ọ̀rẹ́ Wa Ọ̀wọ́n” (J. Barr), 5/15

“Aláìlera Ni Mí Báyìí, àmọ́ Mi Ò Ní Wà Bẹ́ẹ̀ Títí Láé!” (S. van der Monde), 11/15

Bí Ọmọbìnrin Jẹ́fútà (J. Soans), 12/1

Iṣẹ́ Ìsìn Jèhófà Ń Fún Mi Láyọ̀ (F. Rusk), 10/15

Kíka Bíbélì Lójoojúmọ́ Ti Fún Mi Lókun (M. Leroy), 9/15

Mo Bẹ̀rù Ikú, àmọ́ Ìyè “Lọ́pọ̀ Yanturu” Ni Mò Ń Retí Báyìí (P. Gatti), 7/15

Mo Dúpẹ́ Pé Àdánwò Kò Mú Kí N Dẹ́kun Láti Máa Sin Jèhófà (M. de Jonge-van den Heuvel), 1/15

Mo Fẹ́ràn Ìrìn-Àjò àti Eré Ìfarapitú (Z. Dimitrova), 6/1

Mo Ti Jàǹfààní Látinú Àwọn Ìyípadà Tí Mo Ṣe (J. Thompson), 12/15

Mo Ti Rí Ọ̀pọ̀ Ohun Rere (A. Bonno), 4/15

JÈHÓFÀ

Àwọn Òfin Tó Ń Darí Àwọn Nǹkan Tó Wà Lójú Ọ̀run, 7/1

Irọ́ Márùn-ún Táwọn Èèyàn Ń Pa Mọ́ Ọlọ́run, 10/1

Kí Ló Yẹ Kí Àwọn Ọmọdé Kọ́? 8/1

Kí Ni Ọlọ́run Ní Lọ́kàn fún Ilẹ̀ Ayé? 4/1

Kí Nìdí Tí Ọlọ́run Fi Fàyè Gba Ìwà Ibi àti Ìjìyà? 5/1

Kí Nìdí Tó Fi Jẹ́ Pé Àparò Ni Ọlọ́run Fi Bọ́ Àwọn Ọmọ Ísírẹ́lì? 9/1

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Kẹ́kọ̀ọ́ Lọ́dọ̀ Ọlọ́run? 1/1

Ní Ibì Kan Tó Ń Gbé? 8/1

Ǹjẹ́ Ọlọ́run Bìkítà Nípa Rẹ? 1/1

Ǹjẹ́ Ọlọ́run Mọ̀ Pé Ádámù àti Éfà Máa Dẹ́ṣẹ̀? 1/1

Ǹjẹ́ Ọlọ́run Ń Gbé Ẹ̀yà Ìran Kan Ga Ju Òmíràn Lọ? 7/1

Ǹjẹ́ Ọlọ́run Ní Ètò Kan Tó Gbé Kalẹ̀? 6/1

Òfin Ọlọ́run Ń Ṣe Wá Láǹfààní, 1/1

Orúkọ Níbi Àfonífojì (Orílẹ̀-èdè Switzerland), 1/15

Sún Mọ́ Ọlọ́run, 1/1, 2/1, 3/1, 4/1, 5/1, 6/1, 7/1, 8/1, 9/1, 10/1, 11/1, 12/1

Ṣé Ọlọ́run Ló Dá Èṣù? 3/1

Ta Ni Ọlọ́run? 2/1

JÉSÙ KRISTI

Bá A Ṣe Lè Máa Tọ Kristi Aṣáájú Pípé Náà Lẹ́yìn, 5/15

Gbólóhùn Náà “Ìwọ Fúnra Rẹ Wí I,” 6/1

Ibí tí Jésù Ti Wá; Bó Ṣe Gbé Ìgbé Ayé Rẹ̀; Ìdí Tó Fi Kú, 4/1

Ìgbẹ́jọ́, 4/1

Ǹjẹ́ Ó Ṣeé Ṣe Láti Sọ Ní Pàtó Iye Àsọtẹ́lẹ̀ Nípa Mèsáyà? 8/15

Ṣé Òótọ́ Ni Jésù Kú Lórí Àgbélébùú? 3/1

Ta Ni Jésù Kristi? 3/1

Wákàtí Tí Wọ́n Kan Jésù Kristi Mọ́gi, 11/15

Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN

“Agbo Ilé Késárì” (Flp 4:22), 3/1

Àjálù—Ṣé Ọlọ́run Ló Fi Ń Pọ́n Aráyé Lójú? 12/1

Àjọyọ̀ Ìyàsímímọ́ (Jo 10:22), 9/1

Àwọn Àpọ́sítélì Mú Ọ̀pá, Kí Wọ́n sì Wọ Sálúbàtà, 3/15

Àwọn Tó Ń Pààrọ̀ Owó Nínú Tẹ́ńpìlì, 10/1

Bárábà, 4/1

Báwo Làwọn Júù Ṣe Ń Mọ Iye Aago Tó Lù Nígbà Tí Ilẹ̀ Bá Ti Ṣú? 8/1

Báwo Ni Ipò Òṣì Ṣe Máa Dópin? 6/1

Bí Wọ́n Ṣe Ń Rí Owó Ná Sórí Àwọn Nǹkan Tí Wọ́n Ń Ṣe ní Tẹ́ńpìlì, 11/1

Ìdí Tí Sátánì Fi Lo Ejò, 1/1

Igi Ólífì Wúlò Gan-an, 10/1

Ìgbà Wo Ni Wọ́n Pa Jerúsálẹ́mù Run? 10/1, 11/1

“Ìhìn Rere Ìjọba” Náà, 3/1

Ilé Tí Nebukadinésárì Kọ́, 11/1

“Ilẹ̀ Kan Tí Ń Ṣàn fún Wàrà àti Oyin,” 3/1

Ìrètí Wà fún Àwọn Tó Ti Kú, 6/1

Ìrìbọmi fún Àwọn Ọmọ Ọwọ́, 10/1

Irú Àwọn Ẹ̀ṣẹ̀ Wo Ni Wọ́n Lè Torí Rẹ̀ Pààyàn bí Wọ́n Ṣe Pa Jésù? 4/1

Irú Ilé Wo Ló Ṣeé Ṣe Kí Ábúrámù Gbé? 1/1

Jéhù Jà fún Ìjọsìn Mímọ́, 11/15

Késárì, Kí Ló Túmọ̀ Sí? 7/1

Kí Lo Lè Fi Dá Ẹ̀sìn Tòótọ́ Mọ̀? 8/1

Kí Ló Mú Kí Mósè Bínú sí Àwọn Ọmọ Áárónì? (Le 10:16-20), 2/15

Kí Ni Amágẹ́dọ́nì? 9/1

Kí Ni Bíbélì Sọ Nípa Ìbálòpọ̀? 11/1

Kí Ni Ìjọba Ọlọ́run? 7/1

Kí Nìdí Tó Fi Jẹ́ Pé Lẹ́bánónì Ni Sólómọ́nì Ti Kó Igi Gẹdú? 2/1

“Mo Ti Gbà Gbọ́” (Màtá), 4/1

‘Mú Àwọn Àkájọ Ìwé Wá àti Àwọn Ìwé Awọ,’ 6/15

Mú Kí Ìgbésí Ayé Rẹ Dára, 7/1

Ǹjẹ́ Ayé Máa Pa Run ní Ọdún 2012? 12/1

Ǹjẹ́ Ìwàláàyè Títí Láé Nínú Párádísè Máa Súni? 5/1

Ó Fara Da Ìjákulẹ̀ (Sámúẹ́lì), 1/1

Ó Gbèjà Àwọn Èèyàn Ọlọ́run (Ẹ́sítérì), 10/1

Ó Rí Ìtùnú Gbà Lọ́dọ̀ Ọlọ́run (Èlíjà), 7/1

Ojú Wo Ni Àwọn Aṣáájú Ẹ̀sìn Júù ní Ọjọ́ Jésù Fi Ń Wo Àwọn Gbáàtúù? 7/1

Omi Nígbà Ẹ̀ẹ̀rùn Lórílẹ̀-Èdè Ísírẹ́lì, 1/1

“Oríṣi Ohun Ọ̀gbìn Méje” Lára Ohun Ọ̀gbìn Ilẹ̀ Tí Ó Dára Náà, 9/1

Orúkọ Tí Wọ́n Fi Òǹtẹ̀ Lù Sára Amọ̀ Láyé Ìgbàanì, 5/1

Owó (ní àkókò tí wọ́n ń kọ Bíbélì), 5/1

“Òwú Aláwọ̀ Rírẹ̀dòdò Ti Kòkòrò Kókọ́sì,” 12/1

Ọgbà Édẹ́nì, 1/1

Ọkùnrin Kan Tí Ó Tẹ́ Ọkàn Jèhófà Lọ́rùn, 9/1

“Ọmọge, àní Àwọn Ọmọge” (Onw 2:8), 3/15

Pétérù Dé Sílé Ọkùnrin Kan Tó Jẹ́ Oníṣẹ́ Awọ, 6/1

Pípèéṣẹ́, 2/1

Ṣe Bó O Ti Mọ, 6/1

Ṣé Gbogbo Kristẹni Olóòótọ́ Ló Ń Lọ sí Ọ̀run? 6/1

Ṣé Ibi Tí Wọ́n Ti Ń Fi Iná Dáni Lóró Ni Gẹ̀hẹ́nà? 4/1

Ṣé Inú Ọkàn Ni Ìjọba Ọlọ́run Wà? 3/1

Ṣé Ò Ń Múra Sílẹ̀ fún Ọjọ́ Tó Ṣe Pàtàkì Jù Lọ Nínú Ọdún? 2/1

Ṣé Òótọ́ Ni Ábúráhámù Ní Ràkúnmí? 6/15

Ṣé Póòpù Ló “Rọ́pò Pétérù”? 8/180

Ṣíṣú Opó, 3/1

Ta Ló Lè Túmọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀? 12/1

Ta Ló Ń Ṣàkóso Ayé? 9/1

Tẹ́tẹ́ Títa, 3/1

“Títàpá sí Ọ̀pá Kẹ́sẹ́” (Iṣe 26:14), 8/1

Wọ́n Rí Ará Ìlà Oòrùn Éṣíà Kan ní Ítálì Àtijọ́, 1/1