Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Ẹ̀kọ́ Bíbélì

Ẹ̀kọ́ Bíbélì

Ẹ̀kọ́ Bíbélì

ỌMỌ ỌDÚN MẸ́TA ÀTI ÀWỌN TÍ KÒ TÓ BẸ́Ẹ̀

Kọ́lá gbọ́ pé ara ọ̀rẹ́ òun kò yá.

Ó sọ pé: “Mo mọ nǹkan tí màá ṣe.

Mo máa kọ lẹ́tà sí i kí ara rẹ̀ lè yá, màá sì lọ fún un!”

Máa ṣe oore, inú ẹ̀yin méjèèjì yóò sì dùn! 1 Pétérù 3:8

IṢẸ́ ÒBÍ

Ní kí ọmọ rẹ tọ́ka sí:

Ilé Tábìlì Kọ́lá

Oòrùn Ẹyẹ Igi

Dárúkọ ọ̀rẹ́ yín kan tí ara rẹ̀ kò yá, kí o sì bá ọmọ rẹ sọ̀rọ̀ nípa bí ẹ̀yin méjèèjì ṣe lè lọ kí ẹni náà.