Wá Ìdáhùn Àwọn Ìbéèrè Yìí
1. Báwo la ṣe lè dá àwọn ọ̀rẹ́ àlàáfíà mọ̀? (Lúùkù 10:6)
2. Báwo la ṣe lè ran àwọn ọ̀rẹ́ àlàáfíà lọ́wọ́ kí wọ́n lè di ọ̀rẹ́ Ọlọ́run? (Mát. 10:11)
3. Báwo ni Ọmọ Aládé Àlàáfíà ṣe ń ràn wá lọ́wọ́ láti wá àwọn ọ̀rẹ́ àlàáfíà? (Àìsá. 9:6, 7; Mát. 28:20)
4. Báwo la ṣe lè fi hàn pé ọ̀rẹ́ àlàáfíà ni wá? (Sm. 11:5; 2 Tím. 2:24; Jém. 3:17, 18)
5. Báwo làwọn ọ̀rẹ́ àlàáfíà ṣe máa ń ran ara wọn lọ́wọ́? (2 Kọ́r. 6:13)
6. Báwo la ṣe lè “máa fi ire ṣẹ́gun ibi”? (Róòmù 12:2, 6, 10, 18)
© 2022 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
CA-brpgm23-YR