ÀPÓTÍ Ẹ̀KỌ́ 9Ẹ
‘Àkókò Ìmúbọ̀sípò Ohun Gbogbo’
ÌṢE 3:21
Nígbà tí àpọ́sítélì Pétérù ń sọ̀rọ̀ nípa ‘àkókò ìmúbọ̀sípò ohun gbogbo,’ ṣe ló ń sọ tẹ́lẹ̀ nípa àkókò gígùn kan tó máa bẹ̀rẹ̀ látìgbà tí Kristi bá di Ọba títí dé ìparí Ẹgbẹ̀rún Ọdún Ìṣàkóso Kristi.
-
1914—Jésù Kristi di Ọba ní ọ̀run. Àwọn èèyàn Ọlọ́run bẹ̀rẹ̀ sí í kúrò nínú ìgbèkùn tẹ̀mí lọ́dún 1919
Àwọn Ọjọ́ Ìkẹyìn
-
AMÁGẸ́DỌ́NÌ—Ẹgbẹ̀rún Ọdún Ìṣàkóso Kristi bẹ̀rẹ̀, ‘àkókò ìmúbọ̀sípò ohun gbogbo’ sì tún máa mú kí àwọn olóòótọ́ èèyàn lórí ilẹ̀ ayé gbádùn àwọn ìbùkún tara
Ẹgbẹ̀rún Ọdún Ìṣàkóso
-
ẸGBẸ̀RÚN ỌDÚN ÌṢÀKÓSO KRISTI PARÍ—Jésù parí iṣẹ́ rẹ̀ láti mú kí gbogbo nǹkan pa dà bọ̀ sípò, ó sì dá Ìjọba náà pa dà fún Bàbá rẹ̀
Párádísè Títí Ayé
ÌṢÀKÓSO JÉSÙ MÁA MÚ KÍ . . .
-
orúkọ Ọlọ́run pa dà di ológo
-
ara àwọn aláìsàn yá
-
àwọn arúgbó pa dà di ọ̀dọ́
-
àwọn òkú jíǹde
-
àwọn olóòótọ́ èèyàn pa dà di ẹni pípé
-
ayé pa dà di Párádísè