Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Saturday

Saturday

“Ẹ máa fi orúkọ mímọ́ rẹ̀ yangàn. Kí ọkàn àwọn tó ń wá Jèhófà máa yọ̀”​—Sáàmù 105:3

ÀÁRỌ̀

Ọ̀SÁN

  • 1:35 Fídíò Orin

  • 1:45 Orin 76

  • 1:50 Bí Iṣẹ́ Sísọni Di Ọmọ Ẹ̀yìn Ṣe Ń Fún Àwọn Ará Wa Láyọ̀ ní . . .

    • • Áfíríkà

    • • Éṣíà

    • • Yúróòpù

    • • Amẹ́ríkà ti Àríwá

    • • Oceania

    • • Amẹ́ríkà ti Gúúsù

  • 2:35 ÀPÍNSỌ ÀSỌYÉ: Ran Àwọn Tó Ò Ń Kọ́ Lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Lọ́wọ́ Láti . . .

  • 3:30 Orin 110 àti Ìfilọ̀

  • 3:40 FÍÌMÙ: Nehemáyà: “Ìdùnnú Jèhófà Ni Ibi Ààbò Yín”​—Apá Kìíní (Nehemáyà 1:1–6:19)

  • 4:15 Iṣẹ́ Sísọni Di Ọmọ Ẹ̀yìn ti Ìsinsìnyí Ń Múra Wa Sílẹ̀ De ti Ayé Tuntun (Àìsáyà 11:9; Ìṣe 24:15)

  • 4:50 Orin 140 àti Àdúrà Ìparí