Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Atọ́ka Àwọn Àpèjúwe (Àkàwé)

Atọ́ka Àwọn Àpèjúwe (Àkàwé)

Nọ́ńbà kọ̀ọ̀kan dúró fún orí tí àpèjúwe náà wà.

afúnrúgbìn 43

afúnrúgbìn tó sùn 43

àgbébọ̀ adìyẹ ń kó àwọn ọmọ rẹ̀ jọ 110

agbowó orí àti Farisí 94

àgùntàn àti ewúrẹ́ 114

àgùntàn tó sọ nù 63

àjàrà tòótọ́ 120

àlìkámà àti èpò 43

apẹja èèyàn 22

ará Samáríà tó jẹ́ aládùúgbò rere 73

àwọ̀n 43

àwọn ẹyẹ àti òdòdó lílì 35

àwọn méjì tó jẹ gbèsè 40

àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà àjàrà 97

àwọn ọmọ kéékèèké nínú ọjà 39

àwọn tó kọ ìkésíni síbi àsè 83

àwọn tó ń dáko pa ọmọ ẹni tó loko 106

àwọn tó ń dáko, tí wọ́n sì pààyàn 106

ayẹyẹ ìgbéyàwó ọba 107

dírákímà tó sọ nù 85

èso lórí ilẹ̀ tó yàtọ̀ síra 43

ẹ̀mí àìmọ́ tó pa dà wá 42

ẹni tó fẹ́ kọ́ ilé gogoro 84

ẹni tó fọwọ́ lé ohun ìtúlẹ̀ 65

ẹni tó rí dírákímà tó sọ nù 85

ẹnubodè tóóró 35

ẹrú olóòótọ́ àti olóye 111

ẹrú tí kò dárí jini 64

ẹrú tó dé láti oko 89

ẹrú tó ń dúró de ọ̀gá rẹ̀ pé kó dé 78

hóró àlìkámà kú, ó sì so èso 103

hóró músítádì, ìgbàgbọ́ 89

hóró músítádì, Ìjọba 43

igi ọ̀pọ̀tọ́ 79

ilé tí wọ́n kọ́ sórí àpáta 35

ìpìlẹ̀ ilé 35

ìríjú aláìṣòdodo 87

ìríjú olóòótọ́ 78

ìṣúra tí a fi pa mọ́ sínú pápá 43

ìwúkàrà àwọn Farisí 58

ìwúkàrà tí wọ́n pọ̀ mọ́ ìyẹ̀fun 43

iyọ̀ ayé 35

jókòó síbi tó lọ́lá jù 83

mínà 100

ojú abẹ́rẹ́ 96

Olùṣọ́ àgùntàn àtàtà 80

opó kan àti adájọ́ kan 94

ó wu baba láti fúnni ní nǹkan 35

ọba fagi lé gbèsè ńlá tẹ́nì kan jẹ ẹ́ 64

ọba ronú kó tó lọ sójú ogun 84

ọkùnrin ọlọ́rọ̀ àti Lásárù 88

ọkùnrin ọlọ́rọ̀ tó kọ́ ilé ìkẹ́rùsí 77

ọmọ méjì tí wọ́n rán lọ ṣiṣẹ́ nínú ọgbà àjàrà 106

ọmọ onínàákúnàá 86

ọmọ tó sọ nù 86

ọ̀rẹ́ kan tí kò yéé bẹ̀bẹ̀ 74

pe àwọn aláìní síbi àsè 83

péálì kan tó níye lórí gan-an 43

péálì níwájú àwọn ẹlẹ́dẹ̀ 35

pòròpórò nínú ojú arákùnrin 35

ràkúnmí gba ojú abẹ́rẹ́ kọjá 96

rán aṣọ tuntun mọ́ aṣọ tó ti gbó 28

sẹ́ kòkòrò tín-tìn-tín, gbé ràkúnmí mì 109

tálẹ́ńtì 113

wáìnì tuntun, àpò awọ tó ti gbó 28

wọ́n san dínárì fáwọn òṣìṣẹ́ 97

wúńdíá mẹ́wàá 112

ATỌ́KA ÀWỌN ÀPÓTÍ

“Àkókò Tó Láti Wẹ̀ Wọ́n Mọ́” 6

Ìrìn Àjò Tó Ń Múnú Wọn Dùn 10

Àwọn Wo Làwọn Ará Samáríà? 19

Àwọn Tí Ẹ̀mí Èṣù Ń Yọ Lẹ́nu 23

Àpèjúwe Nípa Ààwẹ̀ 28

Jésù Kọ́ni Lóhun Kan Náà Léraléra 35

Òógùn Rẹ̀ Dà Bí Ẹ̀jẹ̀ Tó Ń Kán Sílẹ̀ 123

Pápá Ẹ̀jẹ̀ 127

Bí Wọ́n Ṣe Máa Ń Na Ọ̀daràn 129

“Kàn Án Mọ́gi” 132