Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

APÁ 2

Ìbẹ̀rẹ̀ Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Jésù

‘Wò ó, Ọ̀dọ́ Àgùntàn Ọlọ́run tó kó ẹ̀ṣẹ̀ ayé lọ.’—Jòhánù 1:29

Ìbẹ̀rẹ̀ Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Jésù

NÍ APÁ YÌÍ

ORÍ 12

Jésù Ṣe Ìrìbọmi

Kí nìdí tí Jésù fi ṣèrìbọmi tó bá jẹ́ pé kò dẹ́ṣẹ̀ rí?

ORÍ 13

Kẹ́kọ̀ọ́ Látinú Bí Jésù Ṣe Kojú Àdánwò

Bí Èṣù ṣe dẹ Jésù wò jẹ́ ká mọ nǹkan méjì nípa Èṣù.

ORÍ 14

Jésù Bẹ̀rẹ̀ Sí Í Ní Ọmọ Ẹ̀yìn

Kí ló jẹ́ kó dá àwọn ọmọ ẹ̀yìn mẹ́fà tí Jésù kọ́kọ́ ní lójú pé àwọn ti rí Mèsáyà náà?

ORÍ 15

Jésù Ṣe Iṣẹ́ Ìyanu Àkọ́kọ́

Jésù jẹ́ kí ìyá rẹ̀ mọ̀ pé Baba òun ọ̀run ló ń darí òun báyìí, kì í ṣe ìyá òun.

ORÍ 16

Jésù Ní Ìtara fún Ìjọsìn Tòótọ́

Òfin Ọlọ́run gba àwọn èèyàn láyè láti ra ẹran tí wọ́n máa fi rúbọ ní Jerúsálẹ́mù, kí ló wá dé tí inú fi bí Jésù sí àwọn oníṣòwò tó wà nínú tẹ́ńpìlì?

ORÍ 17

Jésù Kọ́ Nikodémù Lẹ́kọ̀ọ́ ní Òru

Kí ló túmọ̀ sí láti di ‘àtúnbí’?

ORÍ 18

Jòhánù Ń Dín Kù, Àmọ́ Jésù Ń Pọ̀ Sí I

Àwọn ọmọ ẹ̀yìn Jòhánù Arinibọmi ń jowú, bó tilẹ̀ jẹ́ pé Jòhánù ò jowú.

ORÍ 19

Jésù Kọ́ Obìnrin Ará Samáríà Kan Lẹ́kọ̀ọ́

Jésù sọ ohun kan tí kò sọ fún ẹnì kankan rí fún obìnrin náà.