Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

KÍ NI BÍBÉLÌ FI KỌ́NI?

Kí Ni Ọlọ́run Ní Lọ́kàn Tó Fi Dá Ilẹ̀ Ayé? (Apá 3)

Orí kẹta ìwé Kí Ni Bíbélì Fi Kọ́ni Gan-an? ni ìwé ìkẹ́kọ̀ọ́ yìí dá lé.

Ọlọ́run máa lo Ìjọba rẹ̀ láti mú kí ayé yìí rí bó ṣe fẹ́, yóò sì fòpin sí gbogbo ìṣòro tó ń yọ aráyé lẹ́nu.